Iku MohBad: Yọmi Fabiyi atawọn ọdọ maa ṣewọde nileegbimọ aṣofin
Yoruba bọ, wọn ni bi ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ ko nii tan leekanna, bi ẹni a n...
Yoruba bọ, wọn ni bi ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ ko nii tan leekanna, bi ẹni a n...
Ilumọ-ọn-ka arẹwa oṣere tiata, obinrin bọrọkọtọ bii ọka nni, Bisọla Badmus, sọ iwa ti baba ọmọ rẹ, Wasiu Ayinde...
Ṣinkin bii ẹni jẹ tẹtẹ oriire ni inu awọn araalu kan lagbegbe Oke-Ọya ilẹ Naijiria n dun bayii, latari...
Ilumọ-ọn-ka onigbọwọ awọn abẹṣẹẹku-bi-ojo kan, Ọgbẹni Frank Warren ti sọ asọtẹlẹ nipa idije ẹṣẹ kikan to maa waye laipẹ...
Eniola Badmus Omoborty Bo tilẹ jẹ pe ko sẹni to fura pe nnkan kan to le di ija nla...
Priscilla, ọmọ gbajumọ oṣere-binrin ilẹ wa nni, Iyabọ Ojo, rẹwa o si gbafẹ lori ẹrọ ayelujara. Ọpọ awuyewuye lo...
Idris Okunẹyẹ, ọmọkunrin alafẹ to maa n ṣe bii obinrin nni, Bobrisky sọ ohun t’oju rẹ ri l’ẹwọn Kirikiri...
Awọn to n gbero lati gba iwe-aṣẹ irinna siluu oyinbo gbọdọ gbaradi lati san owo igbawe-aṣẹ tuntun, latari bijọba...
Yoruba bọ wọn lọjọ iku laa dere, gbaju-gbaja onkọrin Juju nni, Sunday Iṣọla Adegẹye ti gbogbo eeyan mọ si...
Owe Yoruba to ni iku ti iba pa’ni, to ba ṣi ni fila, o t’ọpẹ, owe naa ti ṣẹ...