Nitori MohBad, Yọmi Fabiyi ti sa kuro ni Naija, o ni wọn fẹẹ pa oun
Yọmi Fabiyi, gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, to tun n ṣiṣẹ ajafẹtọọ-ọmọniyan, ti wọn tun n pe ni Araba...
Yọmi Fabiyi, gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, to tun n ṣiṣẹ ajafẹtọọ-ọmọniyan, ti wọn tun n pe ni Araba...
“Ẹloo, orukọ mi ni Funkẹ Akindele, ti inagijẹ rẹ n jẹ Jẹnifa. Oni ni ayajọ ajọdun ominira Naijiria. Naijiria...
Yoruba bọ, wọn ni ‘isọrọ-nigbesi, isunmusi nigbete-gan-n-gan. Ọrọ yii lo wọ bi gbajugbaja oṣere-binrin onitiata ilẹ wa to lomi...
Lateef Adedimeji Ẹsẹ ko gba ero l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ kẹẹẹdọgbọn, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2024 nile iworan sinima nla kan...
Owe kan nilẹ Yoruba sọ pe: Iku ogun ni i pa akikanju, iku odo ni i pa omuwẹ, iku...
Ọkan ninu owe Yoruba to gbajumọ daadaa lọ bayii: Gele ko dun bii ka mọ ọn we, ka mọ...
Yoruba ko kẹrẹ to ba dọrọ imura, itunraṣe, oge ṣiṣe, ṣiṣe ẹwa lọṣọọ ati irisi. Ko le ma ri...
Yoruba bọ, wọn ni ẹni ti ko gbọ tẹnu ẹga ni yoo sọ pe ẹyẹ oko n pàátó. Irawọ...
Oṣere tiata to rẹwa, to si jafafa nidi iṣẹ rẹ ni Ẹniọla Badmus. Bi ọrọ ṣe da ṣaka lẹnu...
Latari bo ṣe fidi rẹmi niwaju Daniel Dubois, awọn eeyan kan ti n sọ pe Anthony Joshua ko ni...