Eré Ìdárayá
Kúńkúṣì! Ojo owó n rọ̀ f’awọn obinrin agbabọọlu ilẹ wa!
Watch Listen Live TV Orin ti Alaaji Ṣẹfiu Alao, JJC Ọmọ Oko kọ nigba kan pe, “wọn n gbe...
Ayẹyẹ ọjọọbi Baba Olowo, wọn ti ilu Abuja pa ni o!
Watch Listen Live TV Cubana Chief Priest, Obi Cubana fi owo dabira l’Abuja lọjọọbi rẹ Yoruba bọ, wọn ni...
FIFA binu yọ orileede mẹta danu, eyi lohun ti wọn ṣe!
Watch Listen Live TV Ajọ FIFA fi aake nla ṣa orileede mẹta balẹ! Pẹlu iharagaga lawọn ololufẹ ere bọọlu...
Ademọla Lookman binu si kooṣi rẹ, o fesi fun un lakọ-lakọ!
Watch Listen Live TV Ademọla Lookman ni oun ki i sọrọ, amọ kooṣi yii fẹẹ tọwọ bọ oun lẹnu!...
Ọpẹ o, Adebayọ Lookman di agbabọọlu to fakọyọ julọ nilẹ Africa!
Watch Listen Live TV Bi wọn ba n beere ‘ọmọ ti wọn n sọ’ lasiko yii lagbo ere idaraya...
Wọn ti le rẹfirí yii danu, wọn lo fa’gbó lasiko ti ere n lọ lọwọ!
Watch Listen Live TV O jọ pe owe Yoruba to ni ‘owo ti àdá mọ ọn ṣe ni i...
Oṣu kan lẹyin iku iyawo rẹ, agbabọọlu yii fo ṣanlẹ, o ku!
Watch Listen Live TV Agbo ere idaraya nilẹ wa, paapaa ti bọọlu alafẹsẹgba ko daraya lasiko yii, inu ibanujẹ...