Ìròyìn
Ṣe loootọ ni Wumi, iyawo Mohbad, ti loyun ni?
Ọrọ to n ja ranyin bii ina ọyẹ́, to n jó fofo bii ẹwiri alagbedẹ lasiko yii ni ti...
Ẹ ba mi dupẹ gidigidi lọwọ Mercy Aigbe atọkọ ẹ o – Adeniyi Johnson
Ọpọ awọn ololufẹ oṣere tiata mejeeji yii ni ọrọ naa ṣi n ya lẹnu, nitori pe inu okunkun ni...
Eyi lamọran Laide Bakare f’awọn ọmọge asiko
Pẹlu bi ọpọlọpọ awon ọlọmọge ati awọn obinrin ṣe n lakaka lati di ilumọ-ọn-ka ati irawọ nidii iṣẹ aje...
Aluwẹ di ẹni aadọrin ọdun, Tinubu ṣ’adura fun un
Inu idunnu ati idupẹ ni ọkan pataki ninu awọn gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, Alagba Sunday Ọmọbọlanle, ti ọpọ...
O ma ṣe o! Awọn oṣere tiata ṣedaro ọmọ Saidi Balogun to ku lojiji
Titi dasiko ta a wa yii ni ọrọ ibanikẹdun ati aro ṣi n rọ wọle sori ikanni gbajugbaja oṣere...
Nitori MohBad, Yọmi Fabiyi ti sa kuro ni Naija, o ni wọn fẹẹ pa oun
Yọmi Fabiyi, gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, to tun n ṣiṣẹ ajafẹtọọ-ọmọniyan, ti wọn tun n pe ni Araba...
Funkẹ Akindele gba ọmọ Naijiria lamọran pataki lọjọ ọdun ominira
“Ẹloo, orukọ mi ni Funkẹ Akindele, ti inagijẹ rẹ n jẹ Jẹnifa. Oni ni ayajọ ajọdun ominira Naijiria. Naijiria...
Bi mo ṣe pa okoowo pọ mọ ere tiata yii, oju mi ri to! – Mercy Aigbe
Yoruba bọ, wọn ni ẹni ti ko gbọ tẹnu ẹga ni yoo sọ pe ẹyẹ oko n pàátó. Irawọ...
Tori ọrọ to sọ nipa ijọba Tinubu, awọn aye bu Ẹniọla Badmus
Oṣere tiata to rẹwa, to si jafafa nidi iṣẹ rẹ ni Ẹniọla Badmus. Bi ọrọ ṣe da ṣaka lẹnu...