actors
Ṣe loootọ ni Wumi, iyawo Mohbad, ti loyun ni?
Ọrọ to n ja ranyin bii ina ọyẹ́, to n jó fofo bii ẹwiri alagbedẹ lasiko yii ni ti...
Ẹ ba mi dupẹ gidigidi lọwọ Mercy Aigbe atọkọ ẹ o – Adeniyi Johnson
Ọpọ awọn ololufẹ oṣere tiata mejeeji yii ni ọrọ naa ṣi n ya lẹnu, nitori pe inu okunkun ni...
Eyi lamọran Laide Bakare f’awọn ọmọge asiko
Pẹlu bi ọpọlọpọ awon ọlọmọge ati awọn obinrin ṣe n lakaka lati di ilumọ-ọn-ka ati irawọ nidii iṣẹ aje...
Aluwẹ di ẹni aadọrin ọdun, Tinubu ṣ’adura fun un
Inu idunnu ati idupẹ ni ọkan pataki ninu awọn gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, Alagba Sunday Ọmọbọlanle, ti ọpọ...
O ma ṣe o! Awọn oṣere tiata ṣedaro ọmọ Saidi Balogun to ku lojiji
Titi dasiko ta a wa yii ni ọrọ ibanikẹdun ati aro ṣi n rọ wọle sori ikanni gbajugbaja oṣere...
Nitori MohBad, Yọmi Fabiyi ti sa kuro ni Naija, o ni wọn fẹẹ pa oun
Yọmi Fabiyi, gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, to tun n ṣiṣẹ ajafẹtọọ-ọmọniyan, ti wọn tun n pe ni Araba...
Ṣẹyin naa ti gbọ ohun ti Lateef Adedimeji ṣe fawọn ẹlẹgbẹ rẹ?
Lateef Adedimeji Ẹsẹ ko gba ero l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ kẹẹẹdọgbọn, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2024 nile iworan sinima nla kan...
Ṣ’ẹyin naa ti gbọ ohun to ṣẹlẹ laarin Bisọla Badmus ati Wasiu Ayinde?
Ilumọ-ọn-ka arẹwa oṣere tiata, obinrin bọrọkọtọ bii ọka nni, Bisọla Badmus, sọ iwa ti baba ọmọ rẹ, Wasiu Ayinde...