Nitori MohBad, Yọmi Fabiyi ti sa kuro ni Naija, o ni wọn fẹẹ pa oun
Yọmi Fabiyi, gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, to tun n ṣiṣẹ ajafẹtọọ-ọmọniyan, ti wọn tun n pe ni Araba...
Yọmi Fabiyi, gbajumọ oṣere tiata ilẹ wa, to tun n ṣiṣẹ ajafẹtọọ-ọmọniyan, ti wọn tun n pe ni Araba...
“Ẹloo, orukọ mi ni Funkẹ Akindele, ti inagijẹ rẹ n jẹ Jẹnifa. Oni ni ayajọ ajọdun ominira Naijiria. Naijiria...
Lateef Adedimeji Ẹsẹ ko gba ero l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ kẹẹẹdọgbọn, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2024 nile iworan sinima nla kan...
Owe kan nilẹ Yoruba sọ pe: Iku ogun ni i pa akikanju, iku odo ni i pa omuwẹ, iku...
Ọkan ninu owe Yoruba to gbajumọ daadaa lọ bayii: Gele ko dun bii ka mọ ọn we, ka mọ...
Yoruba ko kẹrẹ to ba dọrọ imura, itunraṣe, oge ṣiṣe, ṣiṣe ẹwa lọṣọọ ati irisi. Ko le ma ri...
Yoruba bọ, wọn ni ẹni ti ko gbọ tẹnu ẹga ni yoo sọ pe ẹyẹ oko n pàátó. Irawọ...
Oṣere tiata to rẹwa, to si jafafa nidi iṣẹ rẹ ni Ẹniọla Badmus. Bi ọrọ ṣe da ṣaka lẹnu...
Ilumọ-ọn-ka arẹwa oṣere tiata, obinrin bọrọkọtọ bii ọka nni, Bisọla Badmus, sọ iwa ti baba ọmọ rẹ, Wasiu Ayinde...
Yoruba bọ wọn lọjọ iku laa dere, gbaju-gbaja onkọrin Juju nni, Sunday Iṣọla Adegẹye ti gbogbo eeyan mọ si...